BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Skip Móríwú and continue reading
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
01:23
Fídíò,
Ìdí tí wíwọ ṣòkòtò àwọ̀tẹ́lẹ̀ péńpé 'boxer' sún kò fi dára tó fún ọ
, Duration1,23
05:31
Fídíò,
Ìbọn tí wọ́n yìn sí ọkọ mi kò ràn án, ìgbà tí wọ́n gba àpò ọwọ́ rẹ̀ ni ìbọn tó ràn án – ìyàwó ọmọ ẹgbẹ́ Accord tí wọ́n pa l'Esa Oke ṣalàyé
, Duration5,31
04:07
Fídíò,
Ìkà kọ́ lọmọ ejò, àwa èèyàn là ń kó tiwa bá wọn- Taiwo Okikiola-Ọmọ elejo
, Duration4,07
00:51
Fídíò,
Àǹfààní márùn-ún tó wà nínú kí obìnrin sùn láì wọ pátá
, Duration0,51
03:45
Fídíò,
N kò le fẹ́ ọkùnrin tó lówó, n kò sì le bá ọkùnrin jìyà tàbí ṣe ìyàwó kejì àbí ìkẹta - Eyiyemi Afolayan
, Duration3,45
05:08
Fídíò,
Emi ni obìńrin àkọ́kọ́ tí yóò lo wáyà iná tí kò wúlò láti ṣe iṣẹ́ ọ̀nà àwòrán - Patience Adekunle
, Duration5,08
02:35
Fídíò,
"Ó ṣe ni láàánú pé gómìnà tó fi ebi pa aráàlú, tí kò ṣe dáadáa, ni wọ́n tún fi màgòmágó dá padà síjọba"
, Duration2,35
01:46
Fídíò,
Líla ọwọ́ sí àwọn ẹbí àti ọ̀rẹ́ rẹ lè jẹ́ kí ẹ̀mí ré gùn - Ìwádìí
, Duration1,46
03:29
Fídíò,
Ìjọba Aiyedatiwa fẹ́ lé wa kúrò ní Agọ Ireti, ó tún kọ̀ láti fún wa ní owó oṣù wa – Àwọn olùgbé Agọ Ireti
, Duration3,29
02:38
Fídíò,
Abula: Eré ìdárayá tiwantiwa tí wọ́n fi orúkọ àmàlà, gbẹ̀gìrì àti ewédú sọ tó ti wá ń di gbajúmọ̀ káàkiri
, Duration2,38
04:55
Fídíò,
Ẹ má sá fún ọmọ ẹlẹ́gbẹ́, ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ wọn yóò là – Ifatolani Ayoka, Olórí emèrè ṣàlàyé
, Duration4,55
05:47
Fídíò,
Ademola Adeleke àti APC sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí ara wọn lẹ́yìn ìjà òṣèlú tó wáyé l'Osun
, Duration5,47
01:13
Fídíò,
Ìdí mẹ́rin tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí
, Duration1,13
End of Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
IMF fẹ̀sùn kan ìjọba àpapọ̀ pé ó ná ₦N8.83trn tí kò ní àkọsílẹ̀, ìjọba ṣẹ́, Peter Obi àti Atiku ní kí Tinubu fi ipò sílẹ̀
6 Agẹmo 2026
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ
6 Agẹmo 2026
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
6 Agẹmo 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Èyí lohun tí ìjọba pinnu láti ṣe lẹ́yìn tí omíyalé fojú àwọn olùgbé ìlú Eko rí màbo
2 Agẹmo 2026
Bàbá àti ọmọkùnrin rẹ̀ mẹ́ta, afurasí ajínigbé tó ń fi màálù dídà bojú kó sí gbaga Amotekun l'Ondo
1 Agẹmo 2026
Òṣèré tíátà Mount Zion, Omooba Oluwasegun Oyeyemi jáde láyé
1 Agẹmo 2026
Àwọn ológun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà sẹ́nu iṣẹ́ yawọ ibùgbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní Osun, gba ọ̀pọ̀ fóònù, ohun ìní wọn - Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
1 Agẹmo 2026
Wo òògùn mẹ́fà tó ń dìn agbára ìbálòpọ̀ kù fún ọkùnrin àmọ́ tí ọ̀pọ̀ ṣì ń lò
1 Agẹmo 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Oriyomi Hamzat ń ṣàtìlẹ́yìn fún AMBO olùdíje APC sípò Gómìnà l'Osun? Ohun tí a mọ̀ rèé
1 Agẹmo 2026
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí jàndúkú olóṣèlú tó yìnbọn pa Ezekiel, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá l'Osun
1 Agẹmo 2026
WhatsApp gbé ètò tuntun jáde pẹ̀lú lílo orúkọ fáwọn oníbàárà dìpó nọ́mbà ìbáraẹnisọ̀rọ̀
1 Agẹmo 2026
"Èyi ni ohun tí Olúwa sọ fún mi nípa ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso" – Pásítọ̀ Adeboye
30 Òkùdu 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ìjọba àpapọ̀ kéde ìpínlẹ̀ 26 tí òjò àrọ̀rọ̀dá yóò ti wáyé fún ọ̀sẹ̀ méjìlá èyí tí yóò fa ẹ̀kún omi
2
Ẹ wo ìlúbìnrin tó gbajúmọ̀ tí kò fi ààyè gba ọkùnrin láti máa gbé níbẹ̀
3
Olórí ọmogun Naijiria ṣàlàyé ibi tí iṣẹ́ dé lori ìgbìyànjú láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
4
"N25.5m, àpò ìrẹsì, epo pẹtiró àtàwọn nńkan míì ni ajínigbé gbà lọ́wọ́ wa, káwọn èèyàn wa ní Eda Oniyo tó gba ìtúsílẹ̀, Irọ́ ni, àwa ọlọ́pàá, ológun, Àmọ̀tẹ́kùn ló gbà wọ́n sílẹ̀"
5
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ
6
IMF fẹ̀sùn kan ìjọba àpapọ̀ pé ó ná ₦N8.83trn tí kò ní àkọsílẹ̀, ìjọba ṣẹ́, Peter Obi àti Atiku ní kí Tinubu fi ipò sílẹ̀
7
Bàbá àti ọmọkùnrin rẹ̀ mẹ́ta, afurasí ajínigbé tó ń fi màálù dídà bojú kó sí gbaga Amotekun l'Ondo
8
Ọmọ ọdún méjìlélógún ṣàlàyé bó ṣe jí ara rẹ̀ gbé, tó sì ń bèèrè N25m owó ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ẹbí rẹ̀
9
Àwọn agbébọn ṣèkọlù sáwọn àgbẹ̀ nínú oko, pa mẹ́sàn-án, jí ọ̀pọ̀ gbé lọ
10
Olùṣọ́ Àgùntàn ìjọ CCC ṣàlàyé ìdí tó fi ń ki orí àwọn ọmọ ìjọ sí ábẹ́ aṣọ
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology