BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
02:31
Fídíò,
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Ebola tuntun
, Duration2,31
02:34
Fídíò,
Oronna, jagunjagun tó gbéra láti Oyo lọ tẹ ìlú Ilaro dó
, Duration2,34
02:21
Fídíò,
Olaniyan 'Idamu Industry' Oluwatosin jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí ètò 'Ṣé o láyà?'
, Duration2,21
05:24
Fídíò,
Agbolé Akọni: Mọ̀ nípa Ogboriefon, akọni tí wọ́n rí he lórí àkìtàn tó di jagunjagun ńlá
, Duration5,24
01:40
Fídíò,
Wo bí hòmóònù ṣe ń mú àyípadà bá ìhùwàsí àwọn obìnrin ní ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀
, Duration1,40
04:05
Fídíò,
Mo ti fẹ́ obìnrin rí lágbo tíátà àmọ́ kò ní àṣeyọrí, owó, obìnrin àti agbára ló ń fa gbajúmọ̀ ọkùnrin ṣubú - Abayomi Alvin
, Duration4,05
01:02
Fídíò,
Sola Sobowale àti Lateef Adedimeji sọ̀rọ̀ lórí àmì ẹ̀yẹ AMVCA tí wọn gbà
, Duration1,02
05:59
Fídíò,
Ṣọ́ọ̀ṣì kan rèé tí wọn kií lanu sọ̀rọ̀, ọwọ́ lásán làwọn akọrin, oníwàásù àti olùjọ́sìn fi ń júwe
, Duration5,59
00:52
Fídíò,
Àwọn aṣọ aláràmbarà tí wọ́n lò níbi ayẹyẹ AMVCA
, Duration0,52
03:29
Fídíò,
"Eré ìdárayá ìgbátí ni mo fi ń jẹun, wọ́n ti gbá mi léti rí tí ojú mi ya, mo sojú Nàíjíríà nínú ìdíje àgbáyé"
, Duration3,29
01:30
Fídíò,
"Iṣẹ́ tóo yàn láàyò lè ṣàkóbá fún ìlera ọpọlọ rẹ lọ́jọ́ alẹ́"
, Duration1,30
01:36
Fídíò,
Ìwádìí BBC tú àṣírí àwọn tó ń fi ajá tó ṣèse lú jìbìtì gbowó lórí ayélujára
, Duration1,36
03:25
Fídíò,
Wọ́n pe pásítọ̀ kó wá ṣe ìṣọ́ òru ní ṣọ́ọ̀ṣì ni káwọn agbébọ̀n tó yìnbọn paá – Aráàlú sọ̀rọ̀ lórí ìkọlú àwọn agbébọn sí ṣọ́ọ̀ṣì kan l'Ekiti
, Duration3,25
Ìròyìn tó ṣe kókó
Wo àwọn ìpínlẹ́ àti ìlú tí àwọn agbébọn ti kọlù nílẹ̀ẹ Yorùbá
20 Èbibi 2026
Mo ṣetán láti kojú àwon agbébọn tó wà nínú igbó nílẹ̀ Yorùbá, àṣẹ ìjọba àpapọ̀ ni mò ń dúró dè- Sunday Igboho
20 Èbibi 2026
Wo bí àwọn alátìlẹyìn Arsenal ṣe ń ṣàjọyọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ife ẹ̀yẹ Premier League lẹ́yìn ọdún 22
20 Èbibi 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Gómìnà Seyi Makinde kéde pé òun yóò dupò ààrẹ Naijiria ni 2027
14 Èbibi 2026
Ilé ẹjọ́ ju pásítọ̀ sí ẹ̀wọ̀n gbére fún bíbá ọmọdé mẹ́ta lò pọ̀, ó tún ṣẹ́ oyún fún wọn
15 Èbibi 2026
Ariwo ayọ̀ ní ààfin Ooni ti Ile Ife bí Olori Mariam ṣe bí ìbejì ọkùnrin
15 Èbibi 2026
Làásìgbò bẹ́ sílẹ̀ lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC Oyo, wọ́n ba ilé ẹgbẹ́, dúkìá àwọn olùdíje sípò gómìnà jẹ́
15 Èbibi 2026
Kóòtù sọ Blessing CEO sí àhámọ́, fún ẹ̀sùn lílu jìbìtì N36m
15 Èbibi 2026
Ààrùn Ebola tún gbòde, gbẹ̀mí èèyàn 65
15 Èbibi 2026
Ọ̀pọ̀ èrò n‘Ibadan fẹ̀sùn ajínigbé kan Dókítà kan, wọ́n fẹ́ lú ú pa, dáná sun ọkọ̀ rẹ̀, ọ̀pẹ́ ọlọ́pàá tó dé sásìkò
13 Èbibi 2026
Wo kókó ohun tó ń ṣẹlẹ̀ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú Labour tí wọn fi ní kí Olóòtú Ìjọba UK kọ̀wé fipò sílẹ̀
13 Èbibi 2026
Àlàyé rèé lórí ohun fà á táwọn òṣìṣẹ́ tó ń pèsè omi àti ètò ọ̀gbìn ṣe gunle ìyánṣẹ́lódì
11 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ọmọ ogun ISIS 175 ni a ti ṣekupa –Iléeṣẹ́ ọmọ ogun Naijiria
2
Àwọn ọmọdékùnrin méjì ṣekúpa èèyàn mẹ́ta nínú mọ́ṣáláṣí, pa ara wọn lẹ́yìn rẹ̀
3
"Ọlọrun ti gba ọkọ mi!" Niniola, gbajúmọ olórin tàkasúfèé kéde ikú ọkọ rẹ̀
4
Ọlọ́pàá ṣàlàyé bí àwọn alamí ṣe ran àwọn ajínigbé tó kọlu iléẹ̀kọ́, jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Oyo lọ́wọ́
5
Gómìnà Seyi Makinde ní ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ṣetán láti jíròrò pẹ̀lú àwọn agbébọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́, olùkọ́ gbé kí wọ́n lè tètè padà wálé
6
Èèmọ̀ dé! Èyí làwọn bàbá tó ń ta ọmọ gbowó nítorí àti jẹun
7
Wo àwọn ìpínlẹ́ àti ìlú tí àwọn agbébọn ti kọlù nílẹ̀ẹ Yorùbá
8
Ṣé lóòótọ́ làwọn agbébọn tún yawọ ìlú Ogbomoso? Àlàyé rèé
9
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Eko fẹ́ ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn olórí agbègbè tí wọ́n wó ilé wọn ní Makoko
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 2 Èrèlè 2026
10
Mọ̀ nípa Abu-Bilal al-Minuki, agbéṣùmọ̀mí ti ikọ̀ ológun Amẹ́ríkà àti Nàìjíríà pawọ́pọ̀ ṣekúpa
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology