Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Àkọlé fọ́nrán ohùn, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Published

Huh hun!!!

Ki lo ṣe ẹ to n mi kanlẹ bayii?

Ṣebi ọrọ banki ti mo n lo ti CBN ti gbẹsẹle iwe aṣẹ wọn yii ni, bawo ni mo ṣe fẹ ri owo mi gba

BBC News Yoruba ti gbe iroyin lori ohun ti yoo ṣẹlẹ sowo o rẹ ati bi o ṣe le ri gba soju opo wọn

Jẹ n tara ṣaṣa kan soju opo wọn

'''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''

Ijọba Amẹrika ti pinnu lati ko awọn ọmọ rẹ kuro ni Naijiria

Eyi to n fopin si ajọṣepọ orilẹ ede mejeeji lati gbogunti igbeṣumọmi lẹkun Lake Chad

Amẹrika ni awọn ti yanju bi wọn ṣe n pa awọn Kristẹni lọna aitọ

Awọn akọṣẹmọṣẹ lẹka eto aabo ti ẹ sọ pe Amẹrika ti gbiyanju fun Naijiria

Ṣe ọrọ Boko Haram ti wa di ohun igbagbe ni Naijiria ni?

Kan soju opo wa

''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''

Niṣe ni ọrọ di boolọ o ya fun mi

Bi ina ṣe yọ lọja Bode ni Ibadan

Bi o tilẹ je pe ko si ẹni to fidi ohun to ṣokunfa ijamba naa mulẹ

Ọpọ dukia ati ọja olowo iyebiye lo ba ijamba ina naa lọ