Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Huh hun!!!
Ki lo ṣe ẹ to n mi kanlẹ bayii?
Ṣebi ọrọ banki ti mo n lo ti CBN ti gbẹsẹle iwe aṣẹ wọn yii ni, bawo ni mo ṣe fẹ ri owo mi gba
BBC News Yoruba ti gbe iroyin lori ohun ti yoo ṣẹlẹ sowo o rẹ ati bi o ṣe le ri gba soju opo wọn
Jẹ n tara ṣaṣa kan soju opo wọn
'''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''
Ijọba Amẹrika ti pinnu lati ko awọn ọmọ rẹ kuro ni Naijiria
Eyi to n fopin si ajọṣepọ orilẹ ede mejeeji lati gbogunti igbeṣumọmi lẹkun Lake Chad
Amẹrika ni awọn ti yanju bi wọn ṣe n pa awọn Kristẹni lọna aitọ
Awọn akọṣẹmọṣẹ lẹka eto aabo ti ẹ sọ pe Amẹrika ti gbiyanju fun Naijiria
Ṣe ọrọ Boko Haram ti wa di ohun igbagbe ni Naijiria ni?
Kan soju opo wa
''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''
Niṣe ni ọrọ di boolọ o ya fun mi
Bi ina ṣe yọ lọja Bode ni Ibadan
Bi o tilẹ je pe ko si ẹni to fidi ohun to ṣokunfa ijamba naa mulẹ
Ọpọ dukia ati ọja olowo iyebiye lo ba ijamba ina naa lọ


