BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Coronavirus: Báyìí ni nkan ṣe n lọ ní pápákọ̀ ọkọ̀ òfurufú l'Eko lẹ́yìn tí Coronavirus wọ́lé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo awọn to n wọle, tabi jade kuro ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed lo n gba abẹ ayẹwo kọja
Published
29 Èrèlè 2020
Àkọlé àwòrán,
Yatọ si irinṣẹ ti wọn n mu dani, ẹrọ kan tun wa bi kamẹra to n ṣe ayẹwo awọn eero baalu fun apẹẹrẹ aarun Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Oriṣiriṣi awọn oṣiṣẹ eto ilera lo wa ni ikalẹ ni papakọ ofurufu ilu Eko fun ayẹwo awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Koda, wọn gbe omi aporo kokoro aifojuri 'sanitizer' silẹ fun awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Ati oṣiṣẹ ati eero baalu lo n lo iboju lati ba ara wọn sọrọ nitori Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Kii ṣe ita papakọ ofurufu nikan ni ikiyesara ti n waye, gbagbaagba ni kaluku n boju-bomu ninu ọfiisi.
Àkọlé àwòrán,
Ẹrọ ayaworan wa tun gbe oṣiṣẹ eto ilera kan to wa lẹnu iṣẹ t'oun ti iboju ati ìbọ̀wọ́
Àkọlé àwòrán,
Ṣugbọn o, Coronavirus ko da wiwọle ati jijade ni Naijiria duro ni papakọ ofurufu naa. Kẹti-kẹti ni eero n ya lati wọ baalu.
Àkọlé àwòrán,
Igbesẹ oju lalakan fi n sọri ọhun ko yọ awọn oṣiṣẹ ajọ to n risi iwọle-wọde (Immigration) silẹ. Iboju lawọn naa fi ṣe koju o ma ri ibi.
Skip Móríwú and continue reading
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
04:07
Fídíò,
Ìkà kọ́ lọmọ ejò, àwa èèyàn là ń kó tiwa bá wọn- Taiwo Okikiola-Ọmọ elejo
, Duration4,07
00:51
Fídíò,
Àǹfààní márùn-ún tó wà nínú kí obìnrin sùn láì wọ pátá
, Duration0,51
03:45
Fídíò,
N kò le fẹ́ ọkùnrin tó lówó, n kò sì le bá ọkùnrin jìyà tàbí ṣe ìyàwó kejì àbí ìkẹta - Eyiyemi Afolayan
, Duration3,45
05:08
Fídíò,
Emi ni obìńrin àkọ́kọ́ tí yóò lo wáyà iná tí kò wúlò láti ṣe iṣẹ́ ọ̀nà àwòrán - Patience Adekunle
, Duration5,08
02:35
Fídíò,
"Ó ṣe ni láàánú pé gómìnà tó fi ebi pa aráàlú, tí kò ṣe dáadáa, ni wọ́n tún fi màgòmágó dá padà síjọba"
, Duration2,35
01:46
Fídíò,
Líla ọwọ́ sí àwọn ẹbí àti ọ̀rẹ́ rẹ lè jẹ́ kí ẹ̀mí ré gùn - Ìwádìí
, Duration1,46
03:29
Fídíò,
Ìjọba Aiyedatiwa fẹ́ lé wa kúrò ní Agọ Ireti, ó tún kọ̀ láti fún wa ní owó oṣù wa – Àwọn olùgbé Agọ Ireti
, Duration3,29
02:38
Fídíò,
Abula: Eré ìdárayá tiwantiwa tí wọ́n fi orúkọ àmàlà, gbẹ̀gìrì àti ewédú sọ tó ti wá ń di gbajúmọ̀ káàkiri
, Duration2,38
04:55
Fídíò,
Ẹ má sá fún ọmọ ẹlẹ́gbẹ́, ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ wọn yóò là – Ifatolani Ayoka, Olórí emèrè ṣàlàyé
, Duration4,55
05:47
Fídíò,
Ademola Adeleke àti APC sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí ara wọn lẹ́yìn ìjà òṣèlú tó wáyé l'Osun
, Duration5,47
01:13
Fídíò,
Ìdí mẹ́rin tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí
, Duration1,13
05:36
Fídíò,
"Àwọn agbébọn tó ń jà fún ẹ̀sìn gan ń lo òògùn ìbílẹ̀, ṣé ìjọba le fi 1000 Kùránì àti 1m Bíbélì jagun agbébọn báyìí?"
, Duration5,36
03:47
Fídíò,
Ó pẹ́ tí mo ti sá kúrò nílé, mo rán ara mi ní fásitì, ọjọ́ kan làwọn òbí mi rí mi lórí Tẹlifísàn bíi gbajúmọ̀ akọrin - Shodey
, Duration3,47
End of Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ọkọ̀ òfúrufú tó já lulẹ̀ ní France gbẹ̀mí èèyàn mọ́kànlá
ìṣẹ́jú 30 sẹ́yìn
Mi ò kí ń ṣe aláìmoore bíi Aregbesola, mo máa ṣàtìlẹ́yìn fún Tinubu fún sáà kejì – Igboho
28 Òkùdu 2026
'Èèwọ̀ ni, n kò gbọdọ̀ f'ojú kan ìyá mi láàyè tàbí ní okú'
28 Òkùdu 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ìbejì ló wù wá láti fẹ́ láti ilẹ̀, a ti wà pọ̀ fún ọdún mẹ́wàá, a fẹ́ fẹ́ àwọn ìbejì kan tẹ́lẹ̀ àmọ́ ìwà àti ẹ́jẹ́ wa kò papọ̀ - Ìbejì Oguntoye
23 Òkùdu 2026
Àlàyé lórí báwọn ọ̀dọ́ kan ṣe fi ipá mú abílékọ jáde ní àhámọ́ ọlọ́pàá tí wọ́n sì dáná sun ún
23 Òkùdu 2026
Makinde ti gbalẹ̀ Òrìṣà, mo máa ṣiṣẹ́ tako Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo nínú ètò ìdìbò tó ń bọ̀ - Fayose
23 Òkùdu 2026
Kí ló fa ìbúgbàmù tó wáyé ní Eko tó dá ìbẹ̀rù àti ìdààmú sílẹ̀?
23 Òkùdu 2026
Ẹgbẹ́ Arewa fọnmú lórí ìdúnkookò Sunday Igboho fáwọn Fulani pé yóò lẹ́yìn, Igboho fèsì padà
23 Òkùdu 2026
Ta ni yóò di Olóòtú ìjọba tuntun ní UK, báwo ni wọn yóò ṣe yàn-án?
23 Òkùdu 2026
Amẹrika fòpin sí ìrànwọ́ rẹ̀ láti gbógun ti àrùn HIV/AIDS ní South Africa
22 Òkùdu 2026
Kí ló fà á tí àwọn ọkùnrin fi máa ń lá àlá ìbálòpọ̀?
22 Òkùdu 2026
A ò gba èsì ìbò tó gbé Oyebanji wọlé fún sáà kejì, ètò ìdìbò náà kún fún èrú - AAC
21 Òkùdu 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
'Èèwọ̀ ni, n kò gbọdọ̀ f'ojú kan ìyá mi láàyè tàbí ní okú'
2
Wo ohun tí òfin nọ́mbà ìdánimọ̀ tí Aarẹ ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lù túmọ̀ sí fún ọ
3
Ìjọba Oyo fòpin sí òfin kónílé-ó-gbélé tó gbé kalẹ̀ ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́wàá
4
Mi ò kí ń ṣe aláìmoore bíi Aregbesola, mo máa ṣàtìlẹ́yìn fún Tinubu fún sáà kejì – Igboho
5
A máa tó gba ọkọ̀ òfurufú láti dá ààbò bo ìpínlẹ̀ Oyo, a tún máa ṣí àwọn ilé ẹ̀kọ́ padà láìpẹ́ - Makinde
6
A ṣekúpa òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì iléeṣẹ́ OGTV láti kọ́ ọ lẹ́kọ̀ọ́ ni - Afurasí
7
Tinubu kéde ìgbésẹ̀ tuntun tí ìjọba rẹ̀ ń gbé láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
8
Mọ̀ sí i nípa Ibikunle, Akọni Ìlú Ibadan tó jẹ́ Balogun kan ṣoṣo tó rẹ́yìn Ààrẹ Ọ̀nà Kakaǹfò
9
Ẹgbẹ́ Arewa fọnmú lórí ìdúnkookò Sunday Igboho fáwọn Fulani pé yóò lẹ́yìn, Igboho fèsì padà
10
Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí í wó àwọn ilé tó ti rẹ̀ nítòsí èyí tó wo pa èèyàn mẹ́sàn-án l'Eko
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology