BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eto Iselu
1:00
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 1,00
wákàtí 4 sẹ́yìn
Ọlọ́pàá gbé Baba Adeniyi Adeyemi tíjọba fẹ̀sùn ìdásílẹ̀ ayédèrú iléeṣẹ́ àti àjẹbánu kàn, Gbajabiamila ní òun yóò pe Afurasí náà lẹ́jọ́ N10bn fẹ́sùn ìbanilórúkọ jẹ́
wákàtí 8 sẹ́yìn
Mi ò kìí ṣe olè, àkóbá òṣèlú ni wọ́n ṣe fún mi - Surii Ilupeju
5 Agẹmo 2026
Ọ̀gá ọlọ́pàá Nàìjíríà ṣàbẹ̀wò sí Gómìnà Adeleke, ó ní kò sí jàǹdùkú olóṣèlú tí yóò fi ara ire lọ
4 Agẹmo 2026
Ìjọba Kwara pé Bukola Saraki lẹ́jọ́, wọ́n ló ní Gómìnà Abdulraman kò kàwé délé ẹ̀kọ́ girama
4 Agẹmo 2026
Mo ṣetán láti kojú ìgbẹ́jọ́ láti ṣe àfọ̀mọ́ orúkọ mi - Adeniyi Adeyemi tí ìjọba fẹ̀sùn kàn pé ó ṣe ayédèrú ìwé ìyànsípò rẹ̀
3 Agẹmo 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Oriyomi Hamzat ń ṣàtìlẹ́yìn fún AMBO olùdíje APC sípò Gómìnà l'Osun? Ohun tí a mọ̀ rèé
1 Agẹmo 2026
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí jàndúkú olóṣèlú tó yìnbọn pa Ezekiel, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá l'Osun
1 Agẹmo 2026
5:31
Fídíò,
Ìbọn tí wọ́n yìn sí ọkọ mi kò ràn án, ìgbà tí wọ́n gba àpò ọwọ́ rẹ̀ ni ìbọn tó ràn án – ìyàwó ọmọ ẹgbẹ́ Accord tí wọ́n pa l'Esa Oke ṣalàyé
, Duration 5,31
29 Òkùdu 2026
Teslim Ajimobi, àbúrò Abiola Ajimobi jáde láyé lọ́jọ́ tó pé ọdún mẹ́fà tí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ kú
26 Òkùdu 2026
Wọ́n yìnbọn pa ọkọ mini torí wọ́n ní kó wá rí olóṣèlú APC kan àmọ́ tó yarí kanlẹ̀ - Ìyàwó olóògbé
25 Òkùdu 2026
"Wọ́n yìnbọn pa ọmọ wa ní ṣọ́ọ̀bù ìyá rẹ̀ torí ẹnìkan dé fìlà yẹ́lò tó jẹ́ tẹgbẹ́ Accord l'Osun, mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo"
24 Òkùdu 2026
Kí ló dé tí UK ń pààrọ̀ Olóòtú ìjọba léraléra?
24 Òkùdu 2026
Ta ni yóò di Olóòtú ìjọba tuntun ní UK, báwo ni wọn yóò ṣe yàn-án?
23 Òkùdu 2026
Makinde ti gbalẹ̀ Òrìṣà, mo máa ṣiṣẹ́ tako Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo nínú ètò ìdìbò tó ń bọ̀ - Fayose
23 Òkùdu 2026
A ò gba èsì ìbò tó gbé Oyebanji wọlé fún sáà kejì, ètò ìdìbò náà kún fún èrú - AAC
21 Òkùdu 2026
Ṣé lóòótọ́ nìjọba ìpínlẹ̀ Ogun ti fòfin de ayẹyẹ ìkẹ́kọ̀ọ́jáde ilé ẹ̀kọ́ girama àti alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀? Ohun tí a mọ̀ rèé
21 Òkùdu 2026
Biodun Oyebanji jawe olubori nínú ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti
21 Òkùdu 2026
Ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà buwọ́lu N500bn owó ètò ààbò pàjáwìrì láti ṣẹ́gun ìgbésùnmọ̀mí
19 Òkùdu 2026
Gbogbo kọ̀rọ̀kọ́ndú ìpinlẹ̀ Ekiti ni a ti fi ọlọ́pàá ṣọwọ́ sí fún ètò ìdìbò ọjọ́ Abamẹta - Ọlọ́pàá
19 Òkùdu 2026
"Adedibu ò kú o, a sì ń rí Baálẹ̀ Molete"
18 Òkùdu 2026
Ìjọba Equatorial Guinea kọ̀wé fipò sílẹ̀ lẹ́yìn tó kùnà láti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ
18 Òkùdu 2026
Inú gbogbo èèyàn ìpínlẹ̀ Osun ló dún sí ìdájọ́ tó fààyè gba Accord láti díje, Adeleke ní wọ́n ń fẹ́ - Ìjọba Osun
17 Òkùdu 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá Osun ń hùwà kò kàn mí sí rògbòdìyàn òṣèlú àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ ní ìpínlẹ̀ náà? Ohun tí a mọ̀ rèé
16 Òkùdu 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology