BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ikọ Boko Haram
0:59
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 0,59
12 Ògún 2026
Èló lowó oṣù táwọn ọmogun Naijiria tó wà lójú ìjà ń gbà? Àlàyé rèé
11 Ògún 2026
Ọmogun Naijiria dóòlà èrò ọkọ̀ 33 lọ́wọ́ ajínigbé, bẹ́ sínú igbó láti fọ́wọ́ òfin máwọn jàndùkú agbébọn náà
9 Ògún 2026
Aláboyún méje bí ọmọ kú lọdọ̀ ajínigbé, márùn-ún gbé ọmọ wálé, àgbàdo àti iyọ̀ lóunjẹ wa lẹ́ẹ̀kan lọ́júmọ́ - Àwọn èèyàn ìlú Wọrọ tó gba ìdáǹde lọ́wọ́ ajínigbgbé sọ̀rọ̀
8 Ògún 2026
Wo ẹ̀rùjẹ̀jẹ̀ agbésùnmọ̀mí tí iléeṣẹ́ ológun ń wá, bí wọn ṣe burú sí àti ìdí tó ṣe gbé ẹ̀bùn N60m kalẹ̀ fún ṣíṣe àwárí wọn
7 Ògún 2026
Wo ọgbọ́n àlùmọ̀kọ́rọ́yí tuntun márùn-ún táwọn agbésùnmọ̀mí ń lò láti ṣe ìkọlù apanirun
6 Ògún 2026
Ológun àti ọlọ́pàá kojú agbébọn tó jí èèyàn mẹ́sàn-án gbé, wọ́n rí ọmọdé méje gbà padà, ẹ̀mí agbófinró méjì bọ́
3 Ògún 2026
Ìdí tí mo fi pinnu láti má báwọn jàndùkú tó jí ìyàwó mi gbé nílé ẹ̀kọ́ Esinele sọ̀rọ̀ mọ́ - Ọ̀jọ̀gbọ́n Alamu
28 Agẹmo 2026
Àlàyé rèé lórí bọ́wọ́ ṣe tẹ afurasí sọ́jà tó ń ta aṣọ ọmọ ogun Naijiria fún áwọn agbésùnmọ̀mí
27 Agẹmo 2026
5:16
Fídíò,
Àdó olóró àwọn ajínigbé pa Shuaibu aṣọ́gbóọba lásìkò tó ń lé àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé ní Oriire, àwọn ẹbí rẹ̀ pariwo síta
, Duration 5,16
27 Agẹmo 2026
Ẹkún sọ níbí ìsìn ìrántí fún olóògbé John Olaleye olùkọ́ Oriire táwọn jàndùkú ajínigbé ṣekúpa
26 Agẹmo 2026
Wo ìdí tí Trump ṣe kọ lẹ́tà, kan sáárá sí Tinubu lórí gbígbógun ti ìgbéṣúmọ̀mí
23 Agẹmo 2026
Ajínigbé yọ̀ǹda òkú ìyá, dẹ́rẹ́bà àti ọ̀kan lára ọmọ ìyá mẹ́ta tí wọ́n jí gbé, bèèrè N30m
20 Agẹmo 2026
Àṣìta ìbọn agbésùnmọ̀mí pa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lásìkò táwọn ológun ń dènà ìjínigbé
19 Agẹmo 2026
Wo ẹ̀sùn mẹ́wàá tí wọ́n fi kan àwọn afurasí tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Ogbomoso
18 Agẹmo 2026
Ilé aṣòfin Amẹrika buwọ́lù àbá láti dá ìrànwọ́ Amẹrika fún Naijiria dúró títí tíjọba yóò fi wá ojútùú sí ìṣekúpani àwọn Kristẹni
16 Agẹmo 2026
Ohun tí a mọ̀ nípa bí Boko Haram àti ISWAP ṣe ń lo ìmọ̀ ẹ̀rọ AI fún ìgbésùnmọ̀mí
16 Agẹmo 2026
''Makinde ní láti tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé, àjọ UNO tó ń ké pè kò lè sèwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ náà''
15 Agẹmo 2026
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa John Olaleye, olùkọ́ Oriire kẹta tí àwọn agbésùnmọ̀mí pa ní àhámọ́?
14 Agẹmo 2026
Ilé aṣòfin àgbà ní kí ìjọba yé dáríji àwọn agbéṣùmọ̀mí Boko Haram tó bá juwọ́ sílẹ̀ mọ́
13 Agẹmo 2026
Àwọn ajínigbé de àwọn olùkọ́ ọkùnrin tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso mọ́lẹ̀, wón tún fi aṣọ bò wọ́n lójú fún ọjọ́ mérìndínlọ́gọ́ta - Soun
11 Agẹmo 2026
Ìjìyà tó bá tọ́ sí agbésùnmọ̀mí la máa fún ṣọ́jà tó bá ń dúró de àṣẹ kó tó pa wọ́n- Mínísítà ètò ààbò
10 Agẹmo 2026
Agbèsùnmọ̀mí pa ṣọ́já, dàná sun àgọ́ ọlọ́pàá, iléèwòsàn àti yàrá ìkàwé
9 Agẹmo 2026
Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò
8 Agẹmo 2026
Page
1
nínú
13
1
2
3
4
5
6
7
13
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology